a
1Pt 1.24-25
.
Isaiah 40:6-7
6
a
Ohùn kan wí pé, “Kígbe sókè.”
Èmi sì sọ pé, “Igbe kí ni èmi ó ké?”
“Gbogbo ènìyàn dàbí i koríko,
àti gbogbo ògo wọn dàbí ìtànná igbó.
7
Koríko ń rọ ìtànná sì ń rẹ̀,
nítorí èémí
Olúwa
ń fẹ́ lù wọ́n.
Nítòótọ́ koríko ni àwọn ènìyàn.
Copyright information for
YorBMYO